1 Ọba 11:26 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Bákan náà Jéróbóámù ọmọ Nébátì sì sọ̀tẹ̀ sí ọba. Ó sì jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ìránṣẹ́ Sólómónì, ará Éfúrátì ti Sérédà, ìyá rẹ̀ sì jẹ́ opó, orúkọ rẹ̀ ni Sérúà.

1 Ọba 11

1 Ọba 11:18-35