1 Kọ́ríńtì 10:7 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Kí ẹyin má ṣe sin ère òrìṣà gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti ṣe; gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ pé, “Àwọn ènìyàn náà jókòó láti jẹ àti láti mu, wọ́n sì dìde dúró láti jó.”

1 Kọ́ríńtì 10

1 Kọ́ríńtì 10:2-13