1 Kọ́ríńtì 10:29 Bíbélì Mímọ́ ní Èdè Yorùbá Òde Òní (BMY)

Nǹkan tí ó ṣe pàtàkì ní irú ipò yìí ni ẹ̀rí ọkàn àti èrò ọkùnrin náà, nítorí kì í ṣe ẹ̀rí ọkàn ẹlòmìíràn ní a ó fi dá òmìnira mi lẹ́jọ́.

1 Kọ́ríńtì 10

1 Kọ́ríńtì 10:23-30